Add parallel Print Page Options

36 Ẹyin mọ ọrọ̀ tí Ọlọ́run rán sí àwọn ọmọ Israẹli láti kéde ìròyìn ayọ̀ àlàáfíà nípasẹ̀ Jesu Kristi, ẹni ti ṣe Olúwa ohun gbogbo

Read full chapter

36 You know the message(A) God sent to the people of Israel, announcing the good news(B) of peace(C) through Jesus Christ, who is Lord of all.(D)

Read full chapter

15 (A)Wọ́n ó ha sì ti ṣe wàásù, bí kò ṣe pé a rán wọn? Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé, “Ẹsẹ̀ àwọn tí ń wàásù ìhìnrere àlàáfíà ti dára tó, àwọn tí ń wàásù ìròyìn ayọ̀ ohun rere!”

Read full chapter

15 And how can anyone preach unless they are sent? As it is written: “How beautiful are the feet of those who bring good news!”[a](A)

Read full chapter

Footnotes

  1. Romans 10:15 Isaiah 52:7

15 (A)Tí ẹ sì ti fi ìmúra ìhìnrere àlàáfíà wọ ẹsẹ̀ yín ní bàtà.

Read full chapter

15 and with your feet fitted with the readiness that comes from the gospel of peace.(A)

Read full chapter