Font Size
Ìṣe àwọn Aposteli 19:21
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Ìṣe àwọn Aposteli 19:21
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
21 Ǹjẹ́ bí nǹkan wọ̀nyí tí parí tan, Paulu pinnu nínú ọkàn rẹ̀ pé, nígbà tí òun bá kọjá ní Makedonia àti Akaia, òun ó lọ sí Jerusalẹmu, ó wí pé, “Lẹ́yìn ìgbà tí mo bá dé ibẹ̀, èmi kò lè ṣàìmá dé Romu pẹ̀lú.”
Read full chapter
Ìṣe àwọn Aposteli 24:17
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Ìṣe àwọn Aposteli 24:17
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
17 “Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ọdún púpọ̀, mo wá sí Jerusalẹmu láti mu ẹ̀bùn wá fún àwọn ènìyàn mi fún aláìní àti láti fi ọrẹ lélẹ̀.
Read full chapter
Ìṣe àwọn Aposteli 15:31
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Ìṣe àwọn Aposteli 15:31
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
31 Nígbà tí wọn sì kà á, wọ́n yọ̀ fún ìtùnú náà.
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.