Add parallel Print Page Options

14 (A)Àwa tí rí, a sì jẹ́rìí pé Baba rán Ọmọ rẹ̀ láti jẹ́ Olùgbàlà fún aráyé.

Read full chapter

14 And we have seen and testify(A) that the Father has sent his Son to be the Savior of the world.(B)

Read full chapter

10 ṣùgbọ́n tí a fihàn nísinsin yìí nípa ìfarahàn Jesu Kristi Olùgbàlà wa, ẹni ti ó pa ikú run, tí ó sì mú ìyè àti àìkú wá sí ìmọ́lẹ̀ nípasẹ̀ ìhìnrere.

Read full chapter

10 but it has now been revealed(A) through the appearing of our Savior, Christ Jesus,(B) who has destroyed death(C) and has brought life and immortality to light through the gospel.

Read full chapter