Add parallel Print Page Options

27 Bí ẹnikẹ́ni tí kì í bá ṣe onígbàgbọ́ ba pè yín sí ibi àsè láti jẹun, bá a lọ. Gba ìpè rẹ̀ tí ó bá tẹ́ ọ lọ́rùn. Jẹ ohunkóhun tí ó bá pèsè sílẹ̀ fún àsè náà, má ṣe béèrè ohunkóhun nípa rẹ̀ nítorí ẹ̀rí ọkàn.

Read full chapter

27 If an unbeliever invites you to a meal and you want to go, eat whatever is put before you(A) without raising questions of conscience.

Read full chapter

14 (A)Gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni Olúwa ti fi àṣẹ lélẹ̀ pé, àwọn tí ń wàásù ìhìnrere kí wọn sì máa jẹ́ nípa ìhìnrere.

Read full chapter

14 In the same way, the Lord has commanded that those who preach the gospel should receive their living from the gospel.(A)

Read full chapter

18 (A)Nítorí tí Ìwé mímọ́ wí pé, “Ìwọ kò gbọdọ̀ di màlúù ti ń tẹ ọkà lẹ́nu,” àti pé, “ọ̀yà alágbàṣe tọ́ sí i.”

Read full chapter

18 For Scripture says, “Do not muzzle an ox while it is treading out the grain,”[a](A) and “The worker deserves his wages.”[b](B)

Read full chapter

Footnotes

  1. 1 Timothy 5:18 Deut. 25:4
  2. 1 Timothy 5:18 Luke 10:7

15 San owó iṣẹ́ rẹ̀ ní ọjọ́ kan náà kí ó tó di àṣálẹ́, nítorí ó jẹ́ tálákà, ó sì gbẹ́kẹ̀lé e bí kò ṣe bẹ́ẹ̀ ó lè ké pe Olúwa sí ọ, o sì máa gba ìdálẹ́bi ẹ̀ṣẹ̀.

Read full chapter

15 Pay them their wages each day before sunset, because they are poor(A) and are counting on it.(B) Otherwise they may cry to the Lord against you, and you will be guilty of sin.(C)

Read full chapter