Add parallel Print Page Options

12 (A)Kò sí ní ọ̀run, tí ìwọ kò bá fi wí pé, “Ta ni yóò gòkè lọ sí ọ̀run fún wa, tí yóò sì mú wa fún wa, kí àwa lè gbọ́, kí a sì le ṣe é?” 13 Bẹ́ẹ̀ ni kò sí ní ìhà kejì Òkun, tí ìwọ ìbá fi wí pé, “Ta ni yóò rékọjá Òkun lọ fún wa, tí yóò sì mú un wá fún wa, kí àwa lè gbọ́ ọ, kí a si le ṣe é?”

Read full chapter

12 It is not up in heaven, so that you have to ask, “Who will ascend into heaven(A) to get it and proclaim it to us so we may obey it?”(B) 13 Nor is it beyond the sea,(C) so that you have to ask, “Who will cross the sea to get it and proclaim it to us so we may obey it?”(D)

Read full chapter

30 (A)Ǹjẹ́ kí ni àwa ó ha wí? Pé àwọn Kèfèrí, tí kò lépa òdodo, ọwọ́ wọn tẹ òdodo, ṣùgbọ́n òdodo tí ó ti inú ìgbàlà wá ni.

Read full chapter

Israel’s Unbelief

30 What then shall we say?(A) That the Gentiles, who did not pursue righteousness, have obtained it, a righteousness that is by faith;(B)

Read full chapter