Add parallel Print Page Options

22 (A)Ọlọ́run sì ti fi ohun gbogbo sábẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀, ó sì fi í ṣe orí lórí ohun gbogbo fún ìjọ,

Read full chapter

22 And God placed all things under his feet(A) and appointed him to be head(B) over everything for the church,

Read full chapter

15 (A)Ṣùgbọ́n ká a máa sọ òtítọ́ ní ìfẹ́, kí a lè máa dàgbàsókè nínú rẹ̀ ní ohun gbogbo ẹni tí i ṣe orí, àní Kristi.

Read full chapter

15 Instead, speaking the truth in love,(A) we will grow to become in every respect the mature body of him who is the head,(B) that is, Christ.

Read full chapter

23 Nítorí pé ọkọ ni ó ń ṣe orí aya, gẹ́gẹ́ bí Kristi tí i ṣe orí ìjọ, tí òun si ń ṣe ara rẹ̀, Òun sì ni Olùgbàlà rẹ̀.

Read full chapter

23 For the husband is the head of the wife as Christ is the head of the church,(A) his body, of which he is the Savior.

Read full chapter

Ẹni ti ó sọ fún wa nípa ìfẹ́ yín nínú ẹ̀mí.

Read full chapter

and who also told us of your love in the Spirit.(A)

Read full chapter

19 (A)Wọn ti sọ ìdàpọ̀ wọn pẹ̀lú ẹni tí i ṣe orí nu, láti ọ̀dọ̀ ẹni tí a ń ti ipa oríkèé àti iṣan pèsè fún gbogbo ara, ti a sì ń so ó ṣọ̀kan pọ̀, tí ó sì ń dàgbà nípa ìmísí Ọlọ́run.

Read full chapter

19 They have lost connection with the head,(A) from whom the whole body,(B) supported and held together by its ligaments and sinews, grows as God causes it to grow.(C)

Read full chapter