Add parallel Print Page Options

Ètùtù owó

11 (A)Nígbà náà ni Olúwa wí fún Mose pé, 12 “Nígbà tí ìwọ bá ka iye àwọn ọmọ Israẹli láti mọ iye wọn, ẹnìkọ̀ọ̀kan wọn gbọdọ̀ mú ìràpadà ọkàn rẹ̀ wá fún Olúwa ní ìgbà tí o bá ka iye wọn. Nígbà náà ni àjàkálẹ̀-ààrùn kì yóò súnmọ́ wọn, nígbà tí o bá ń ka iye wọn. 13 Olúkúlùkù ẹrù tí ó bá kọjá lọ sọ́dọ̀ àwọn tí a ti kà yóò san ìdajì ṣékélì, gẹ́gẹ́ bí ṣékélì ibi mímọ́, èyí tí ó wọn ogún gera. Ìdajì ṣékélì yìí ní ọrẹ fún Olúwa. 14 Gbogbo àwọn tí ó bá kọjá sínú àwọn tí a kà láti ẹni ogún ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ, ni yóò fi ọrẹ fún Olúwa. 15 Àwọn olówó kì yóò san ju ìdajì ṣékélì lọ, àwọn tálákà kò sì gbọdọ̀ dín ní ìdajì ṣékélì nígbà tí ẹ̀yin bá mú ọrẹ wá fún Olúwa láti ṣe ètùtù fún ọkàn yín. 16 Ìwọ yóò sì gba owó ètùtù náà lọ́wọ́ àwọn ọmọ Israẹli, ìwọ yóò sì fi lélẹ̀ fún ìsìn àgọ́ àjọ. Yóò jẹ́ ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli níwájú Olúwa, láti ṣe ètùtù fún ọkàn yín.”

Read full chapter

Atonement Money

11 Then the Lord said to Moses, 12 “When you take a census(A) of the Israelites to count them, each one must pay the Lord a ransom(B) for his life at the time he is counted. Then no plague(C) will come on them when you number them. 13 Each one who crosses over to those already counted is to give a half shekel,[a] according to the sanctuary shekel,(D) which weighs twenty gerahs. This half shekel is an offering to the Lord. 14 All who cross over, those twenty years old or more,(E) are to give an offering to the Lord. 15 The rich are not to give more than a half shekel and the poor are not to give less(F) when you make the offering to the Lord to atone for your lives. 16 Receive the atonement(G) money from the Israelites and use it for the service of the tent of meeting.(H) It will be a memorial(I) for the Israelites before the Lord, making atonement for your lives.”

Read full chapter

Footnotes

  1. Exodus 30:13 That is, about 1/5 ounce or about 5.8 grams; also in verse 15