Add parallel Print Page Options

Ère òrìṣà wúrà

32 (A)Nígbà tí àwọn ènìyàn rí i pé Mose pẹ́ kí ó tó sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè wá, wọn péjọ yí Aaroni ká, wọ́n sì wí pé, “Wá, dá òrìṣà tí yóò máa ṣáájú wa fún wa. Bí ó ṣe ti Mose tí ó mú wa jáde láti Ejibiti wá, àwa kò mọ́ ohun tí ó ti ṣẹlẹ̀ sí i.”

Read full chapter

The Golden Calf

32 When the people saw that Moses was so long in coming down from the mountain,(A) they gathered around Aaron and said, “Come, make us gods[a] who will go before(B) us. As for this fellow Moses who brought us up out of Egypt, we don’t know what has happened to him.”(C)

Read full chapter

Footnotes

  1. Exodus 32:1 Or a god; also in verses 23 and 31

23 (A)Wọ́n sọ fún mi pé, ‘Ṣe òrìṣà fún wa, tí yóò máa ṣáájú wa. Bí ó ṣe ti Mose ẹni tí ó mú wa jáde láti Ejibiti wá àwa kò mọ ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí i.’

Read full chapter

23 They said to me, ‘Make us gods who will go before us. As for this fellow Moses who brought us up out of Egypt, we don’t know what has happened to him.’(A)

Read full chapter