Add parallel Print Page Options

32 (A)Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, jọ̀wọ́ dárí ẹ̀ṣẹ̀ wọn jì wọ́n ṣùgbọ́n tí kò bá sì ṣe bẹ́ẹ̀, pa orúkọ mi rẹ́ kúrò nínú ìwé tí ìwọ ti kọ.”

Read full chapter

32 But now, please forgive their sin(A)—but if not, then blot me(B) out of the book(C) you have written.”

Read full chapter

28 (A)Jẹ́ kí a yọ wọ́n kúrò nínú ìwé ìyè
    kí á má kà wọ́n pẹ̀lú àwọn olódodo.

Read full chapter

28 May they be blotted out of the book of life(A)
    and not be listed with the righteous.(B)

Read full chapter

Ìgbà ìkẹyìn

12 (A)“Ní àkókò náà, ni Mikaeli, ọmọ-aládé ńlá, ẹni tí o ń dáàbò bo àwọn ènìyàn an rẹ̀ yóò dìde. Àkókò ìpọ́njú yóò wà, irú èyí tí kò tí ì ṣẹlẹ̀ rí láti ìbẹ̀rẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè títí di àkókò náà. Ṣùgbọ́n ní àkókò náà àwọn ènìyàn rẹ̀, gbogbo àwọn tí a bá ti rí orúkọ wọn nínú ìwé ni a ó gbàlà.

Read full chapter

The End Times

12 “At that time Michael,(A) the great prince who protects your people, will arise. There will be a time of distress(B) such as has not happened from the beginning of nations until then. But at that time your people—everyone whose name is found written in the book(C)—will be delivered.(D)

Read full chapter

(A)Mo sì bẹ̀ yin pẹ̀lú bí alájọru àjàgà mi tòótọ́, ran àwọn obìnrin wọ̀nyí lọ́wọ́, nítorí wọn bá mi ṣiṣẹ́ pọ̀ ní ìfẹ̀gbẹ́-kẹ̀gbẹ́ nínú ìhìnrere, àti Klementi pẹ̀lú, àti àwọn olùbáṣiṣẹ́ mi yòókù pẹ̀lú, orúkọ àwọn tí ń bẹ nínú ìwé ìyè.

Read full chapter

Yes, and I ask you, my true companion, help these women since they have contended at my side in the cause of the gospel, along with Clement and the rest of my co-workers,(A) whose names are in the book of life.(B)

Read full chapter

23 Si àjọ ńlá tí ìjọ àkọ́bí tí a ti kọ orúkọ wọn ni ọ̀run, àti sọ́dọ̀ Ọlọ́run onídàájọ́ gbogbo ènìyàn, àti sọ́dọ̀ àwọn ẹ̀mí olóòtítọ́ ènìyàn tí a ṣe ni àṣepé, o

Read full chapter

23 to the church of the firstborn,(A) whose names are written in heaven.(B) You have come to God, the Judge of all,(C) to the spirits of the righteous made perfect,(D)

Read full chapter

(A)Ẹni tí ó bá ṣẹ́gun, òun náà ni a ó fi aṣọ funfun wọ̀; èmi kì yóò pa orúkọ rẹ̀ kúrò nínú ìwé ìyè, ṣùgbọ́n èmi yóò jẹ́wọ́ orúkọ rẹ̀ níwájú Baba mi, àti níwájú àwọn angẹli rẹ̀.

Read full chapter

The one who is victorious(A) will, like them, be dressed in white.(B) I will never blot out the name of that person from the book of life,(C) but will acknowledge that name before my Father(D) and his angels.

Read full chapter

Gbogbo àwọn tí ń gbé orí ilẹ̀ ayé yóò sì máa sìn ín, olúkúlùkù ẹni tí a kò kọ orúkọ rẹ̀, sínú ìwé ìyè Ọ̀dọ́-Àgùntàn tí a tí pa láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé.

Read full chapter

All inhabitants of the earth(A) will worship the beast—all whose names have not been written in the Lamb’s book of life,(B) the Lamb(C) who was slain from the creation of the world.[a](D)

Read full chapter

Footnotes

  1. Revelation 13:8 Or written from the creation of the world in the book of life belonging to the Lamb who was slain

27 (A)Ohun aláìmọ́ kan ki yóò sì wọ inú rẹ̀ rárá, tàbí ohun tí ń ṣiṣẹ́ ìríra àti èké; bí kò ṣe àwọn tí a kọ sínú ìwé ìyè Ọ̀dọ́-àgùntàn.

Read full chapter

27 Nothing impure will ever enter it, nor will anyone who does what is shameful or deceitful,(A) but only those whose names are written in the Lamb’s book of life.(B)

Read full chapter