Eksodu 32:32
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
32 (A)Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, jọ̀wọ́ dárí ẹ̀ṣẹ̀ wọn jì wọ́n ṣùgbọ́n tí kò bá sì ṣe bẹ́ẹ̀, pa orúkọ mi rẹ́ kúrò nínú ìwé tí ìwọ ti kọ.”
Read full chapter
Exodus 32:32
New International Version
32 But now, please forgive their sin(A)—but if not, then blot me(B) out of the book(C) you have written.”
Saamu 69:28
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
28 (A)Jẹ́ kí a yọ wọ́n kúrò nínú ìwé ìyè
kí á má kà wọ́n pẹ̀lú àwọn olódodo.
Psalm 69:28
New International Version
Daniẹli 12:1
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Ìgbà ìkẹyìn
12 (A)“Ní àkókò náà, ni Mikaeli, ọmọ-aládé ńlá, ẹni tí o ń dáàbò bo àwọn ènìyàn an rẹ̀ yóò dìde. Àkókò ìpọ́njú yóò wà, irú èyí tí kò tí ì ṣẹlẹ̀ rí láti ìbẹ̀rẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè títí di àkókò náà. Ṣùgbọ́n ní àkókò náà àwọn ènìyàn rẹ̀, gbogbo àwọn tí a bá ti rí orúkọ wọn nínú ìwé ni a ó gbàlà.
Read full chapter
Daniel 12:1
New International Version
The End Times
12 “At that time Michael,(A) the great prince who protects your people, will arise. There will be a time of distress(B) such as has not happened from the beginning of nations until then. But at that time your people—everyone whose name is found written in the book(C)—will be delivered.(D)
Filipi 4:3
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
3 (A)Mo sì bẹ̀ yin pẹ̀lú bí alájọru àjàgà mi tòótọ́, ran àwọn obìnrin wọ̀nyí lọ́wọ́, nítorí wọn bá mi ṣiṣẹ́ pọ̀ ní ìfẹ̀gbẹ́-kẹ̀gbẹ́ nínú ìhìnrere, àti Klementi pẹ̀lú, àti àwọn olùbáṣiṣẹ́ mi yòókù pẹ̀lú, orúkọ àwọn tí ń bẹ nínú ìwé ìyè.
Read full chapter
Philippians 4:3
New International Version
3 Yes, and I ask you, my true companion, help these women since they have contended at my side in the cause of the gospel, along with Clement and the rest of my co-workers,(A) whose names are in the book of life.(B)
Heberu 12:23
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
23 Si àjọ ńlá tí ìjọ àkọ́bí tí a ti kọ orúkọ wọn ni ọ̀run, àti sọ́dọ̀ Ọlọ́run onídàájọ́ gbogbo ènìyàn, àti sọ́dọ̀ àwọn ẹ̀mí olóòtítọ́ ènìyàn tí a ṣe ni àṣepé, o
Read full chapter
Hebrews 12:23
New International Version
23 to the church of the firstborn,(A) whose names are written in heaven.(B) You have come to God, the Judge of all,(C) to the spirits of the righteous made perfect,(D)
Ìfihàn 3:5
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
5 (A)Ẹni tí ó bá ṣẹ́gun, òun náà ni a ó fi aṣọ funfun wọ̀; èmi kì yóò pa orúkọ rẹ̀ kúrò nínú ìwé ìyè, ṣùgbọ́n èmi yóò jẹ́wọ́ orúkọ rẹ̀ níwájú Baba mi, àti níwájú àwọn angẹli rẹ̀.
Read full chapter
Revelation 3:5
New International Version
Ìfihàn 13:8
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
8 Gbogbo àwọn tí ń gbé orí ilẹ̀ ayé yóò sì máa sìn ín, olúkúlùkù ẹni tí a kò kọ orúkọ rẹ̀, sínú ìwé ìyè Ọ̀dọ́-Àgùntàn tí a tí pa láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé.
Read full chapter
Revelation 13:8
New International Version
8 All inhabitants of the earth(A) will worship the beast—all whose names have not been written in the Lamb’s book of life,(B) the Lamb(C) who was slain from the creation of the world.[a](D)
Footnotes
- Revelation 13:8 Or written from the creation of the world in the book of life belonging to the Lamb who was slain
Ìfihàn 21:27
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
27 (A)Ohun aláìmọ́ kan ki yóò sì wọ inú rẹ̀ rárá, tàbí ohun tí ń ṣiṣẹ́ ìríra àti èké; bí kò ṣe àwọn tí a kọ sínú ìwé ìyè Ọ̀dọ́-àgùntàn.
Read full chapter
Revelation 21:27
New International Version
27 Nothing impure will ever enter it, nor will anyone who does what is shameful or deceitful,(A) but only those whose names are written in the Lamb’s book of life.(B)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.
Holy Bible, New International Version®, NIV® Copyright ©1973, 1978, 1984, 2011 by Biblica, Inc.® Used by permission. All rights reserved worldwide.
NIV Reverse Interlinear Bible: English to Hebrew and English to Greek. Copyright © 2019 by Zondervan.