Add parallel Print Page Options

32 (A)Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, jọ̀wọ́ dárí ẹ̀ṣẹ̀ wọn jì wọ́n ṣùgbọ́n tí kò bá sì ṣe bẹ́ẹ̀, pa orúkọ mi rẹ́ kúrò nínú ìwé tí ìwọ ti kọ.”

Read full chapter

32 But now, please forgive their sin(A)—but if not, then blot me(B) out of the book(C) you have written.”

Read full chapter

28 (A)Jẹ́ kí a yọ wọ́n kúrò nínú ìwé ìyè
    kí á má kà wọ́n pẹ̀lú àwọn olódodo.

Read full chapter

28 May they be blotted out of the book of life(A)
    and not be listed with the righteous.(B)

Read full chapter

Ìgbà ìkẹyìn

12 (A)“Ní àkókò náà, ni Mikaeli, ọmọ-aládé ńlá, ẹni tí o ń dáàbò bo àwọn ènìyàn an rẹ̀ yóò dìde. Àkókò ìpọ́njú yóò wà, irú èyí tí kò tí ì ṣẹlẹ̀ rí láti ìbẹ̀rẹ̀ àwọn orílẹ̀-èdè títí di àkókò náà. Ṣùgbọ́n ní àkókò náà àwọn ènìyàn rẹ̀, gbogbo àwọn tí a bá ti rí orúkọ wọn nínú ìwé ni a ó gbàlà.

Read full chapter

The End Times

12 “At that time Michael,(A) the great prince who protects your people, will arise. There will be a time of distress(B) such as has not happened from the beginning of nations until then. But at that time your people—everyone whose name is found written in the book(C)—will be delivered.(D)

Read full chapter

32 “Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́wọ́ mi níwájú ènìyàn, òun náà ni èmi yóò jẹ́wọ́ rẹ̀ níwájú Baba mi ní ọ̀run.

Read full chapter

32 “Whoever acknowledges me before others,(A) I will also acknowledge before my Father in heaven.

Read full chapter