Add parallel Print Page Options

23 (A)Èmi yóò fi olùṣọ́-àgùntàn kan ṣe olórí wọn, ìránṣẹ́ mi Dafidi, òun yóò sì tọ́jú wọn; Òun yóò bọ́ wọn yóò sì jẹ́ olùṣọ́-àgùntàn wọn.

Read full chapter

23 I will place over them one shepherd, my servant David, and he will tend(A) them; he will tend them and be their shepherd.(B)

Read full chapter

    (A)Ó mú mi dùbúlẹ̀ sí ibi pápá oko tútù
Ó mú mi lọ sí ibi omi dídákẹ́ rọ́rọ́;

Read full chapter

    He makes me lie down in green pastures,
he leads me beside quiet waters,(A)

Read full chapter

(A)Òun yóò sì gbé ikú mì títí láé.
    Olúwa Olódùmarè yóò sì nu gbogbo omijé nù,
kúrò ní ojú gbogbo wọn;
    Òun yóò sì mú ẹ̀gàn àwọn ènìyàn rẹ̀ kúrò
ní gbogbo ilẹ̀ ayé.
    Olúwa ni ó ti sọ ọ́.

Read full chapter

    he will swallow up death(A) forever.
The Sovereign Lord will wipe away the tears(B)
    from all faces;
he will remove his people’s disgrace(C)
    from all the earth.
The Lord has spoken.(D)

Read full chapter