Add parallel Print Page Options

21 Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run mú kí ọkùnrin náà sùn fọnfọn; nígbà tí ó sì ń sùn, Ọlọ́run yọ egungun ìhà rẹ̀ kan, ó sì fi ẹran-ara bò ó padà. 22 Olúwa Ọlọ́run sì dá obìnrin láti inú egungun tí ó yọ ní ìhà ọkùnrin náà, Ó sì mu obìnrin náà tọ̀ ọ́ wá.

23 Ọkùnrin náà sì wí pé,

“Èyí ni egungun láti inú egungun mi
    àti ẹran-ara nínú ẹran-ara mi;
‘obìnrin’ ni a ó máa pè é,
    nítorí a mú un jáde láti ara ọkùnrin.”

Read full chapter

21 So the Lord God caused the man to fall into a deep sleep;(A) and while he was sleeping, he took one of the man’s ribs[a] and then closed up the place with flesh. 22 Then the Lord God made a woman from the rib[b](B) he had taken out of the man, and he brought her to the man.

23 The man said,

“This is now bone of my bones
    and flesh of my flesh;(C)
she shall be called(D) ‘woman,’
    for she was taken out of man.(E)

Read full chapter

Footnotes

  1. Genesis 2:21 Or took part of the man’s side
  2. Genesis 2:22 Or part