Add parallel Print Page Options

29 Bí ẹ̀yin bá sì jẹ́ ti Kristi, ǹjẹ́ ẹ̀yin ní irú-ọmọ Abrahamu, àti àrólé gẹ́gẹ́ bí ìlérí.

Read full chapter

29 If you belong to Christ,(A) then you are Abraham’s seed,(B) and heirs(C) according to the promise.(D)

Read full chapter

Nítorí náà ìwọ kì í ṣe ẹrú, bí kò ṣe ọmọ; àti bí ìwọ bá ń ṣe ọmọ, ǹjẹ́ ìwọ di àrólé Ọlọ́run nípasẹ̀ Kristi.

Read full chapter

So you are no longer a slave, but God’s child; and since you are his child, God has made you also an heir.(A)

Read full chapter

Nítorí pé bí àwa ti pín nínú ìjìyà Kristi, gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ nì ìtùnú wa dí púpọ̀ pẹ̀lú nípa Kristi.

Read full chapter

For just as we share abundantly in the sufferings of Christ,(A) so also our comfort abounds through Christ.

Read full chapter

Àti pé ìrètí wa nípa tiyín dúró ṣinṣin, àwa si mọ̀ pé, bí ẹ̀yin ti jẹ alábápín nínú ìyà wa, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin ń pín nínú ìtùnú náà pẹ̀lú.

Read full chapter

And our hope for you is firm, because we know that just as you share in our sufferings,(A) so also you share in our comfort.

Read full chapter

12 Bí àwa bá faradà,
    àwa ó sì bá a jẹ ọba:
Bí àwa bá sẹ́ ẹ,
    òun náà yóò sì sẹ́ wa.

Read full chapter

12 if we endure,
    we will also reign with him.(A)
If we disown him,
    he will also disown us;(B)

Read full chapter

13 Ṣùgbọ́n níwọ̀n bí ẹ̀yin tí jẹ́ alábápín ìyà Kristi, ẹ máa yọ̀, kí ẹ̀yin lè yọ ayọ̀ púpọ̀ nígbà tí a bá fi ògo rẹ̀ hàn.

Read full chapter

13 But rejoice(A) inasmuch as you participate in the sufferings of Christ,(B) so that you may be overjoyed when his glory is revealed.(C)

Read full chapter