Add parallel Print Page Options

10 Ègbé ni fún àwọn ti ń ṣe òfin àìṣòdodo
láti dún àwọn aláìní ní ẹ̀tọ́ wọn
    àti láti fa ọwọ́ ìdájọ́ sẹ́yìn kúrò
níwájú àwọn olùpọ́njú ènìyàn mi,
    Wọ́n sọ àwọn ọ̀pọ̀ di ìjẹ fún wọn.
    Wọ́n sì ń ja àwọn aláìní baba lólè.
Kí ni ìwọ yóò ṣe ní ọjọ́ ìṣirò
    nígbà tí ìparun bá ti ọ̀nà jíjìn wá?
Ta ni ìwọ yóò sá tọ̀ fún ìrànlọ́wọ́?
    Níbo ni ìwọ yóò fi ọrọ̀ rẹ sí?
Ohunkóhun kò ní ṣẹ́kù mọ́ bí kò ṣe láti tẹ̀ ba láàrín àwọn ìgbèkùn
    tàbí kí o ṣubú sáàrín àwọn tí a pa.

Pẹ̀lú gbogbo nǹkan wọ̀nyí, ìbínú rẹ̀ kò kúrò,
    ọwọ́ rẹ̀ sì tún gbé sókè.

Ìdájọ́ Ọlọ́run Lórí Asiria

(A)“Ègbé ni fún àwọn ará Asiria, ọ̀gọ ìbínú mi,
    ní ọwọ́ ẹni tí kùmọ̀ ìbínú mi wà!
Mo rán an sí orílẹ̀-èdè aláìní Ọlọ́run
    Mo dojú rẹ̀ kọ àwọn ènìyàn tí ó mú mi bínú
láti já ẹrù gbà, àti láti kó ìkógun
    láti tẹ̀ mọ́lẹ̀ bí amọ̀ ní ojú òpópó.
Ṣùgbọ́n, èyí kì í ṣe ohun tí ó fẹ́ ṣe,
    èyí kọ́ ni ohun tí ó ní lọ́kàn;
èrò rẹ̀ ni láti parun,
    láti fi òpin sí ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè.
‘Kì í ha ṣe pé ọba ni gbogbo àwọn aláṣẹ mi?’ ni Olúwa wí.
‘Kì í ha ṣe pé Kalno dàbí i Karkemiṣi?
    Hamati kò ha dàbí i Arpadi,
    àti Samaria bí i Damasku?
10 Gẹ́gẹ́ bí ọwọ́ mi ti gbá ìjọba àwọn òrìṣà mú,
    ìjọba tí ère rẹ̀ pọ̀ ju ti Jerusalẹmu àti Samaria lọ.
11 Èmi kì yóò a bá Jerusalẹmu wí àti àwọn ère rẹ̀?’ ”
    Gẹ́gẹ́ bí mo ṣe ṣe sí Samaria àti àwọn ère rẹ̀?

12 Nígbà tí Olúwa ti ṣe iṣẹ́ rẹ̀ sí òkè Sioni àti Jerusalẹmu, yóò sọ wí pé, “Èmi yóò fi ìyà jẹ ọba Asiria nítorí gààrù àyà rẹ̀ àti ìgbéraga ojú rẹ̀. 13 Nítorí ó sọ pé:

“ ‘Pẹ̀lú agbára ọwọ́ mi ni mo fi ṣe èyí
    àti pẹ̀lú ọgbọ́n ọ̀n mi, nítorí mo ní òye.
Mo mú ààlà àwọn orílẹ̀-èdè kúrò,
    Mo sì ti kó ìṣúra wọn.
    Gẹ́gẹ́ bí alágbára kan, mo borí àwọn ọba wọn.
14 Bí ènìyàn ti í tọwọ́ bọ ìtẹ́ ẹyẹ,
    bẹ́ẹ̀ ni ọwọ́ mi tẹ ọrọ̀ àwọn orílẹ̀-èdè.
Bí ènìyàn ti í kó ẹyin tí a kọ̀sílẹ̀,
    bẹ́ẹ̀ ni mo kó àwọn orílẹ̀-èdè
kò sí èyí tí ó fi apá lu apá,
    tàbí kí ó ya ẹnu láti dún.’ ”

15 Ǹjẹ́ àáké le gbé ara rẹ̀ sókè kọjá ẹni tí ó ń fì í,
    tàbí kí ayùn fọ́nnu sí ẹni tí ó ń lò ó?
Àfi bí ẹni pé ọ̀pá ó na ẹni tí ó gbé e sókè,
    tàbí kí kùmọ̀ lu èyí tí kì í ṣe igi.
16 Nítorí náà, ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun,
    yóò rán ààrùn ìrẹ̀dànù sórí
àwọn akíkanjú jagunjagun,
    lábẹ́ ògo rẹ̀ ni iná kan yóò ti sọ
    gẹ́gẹ́ bí iná ajónirun.
17 Ìmọ́lẹ̀ Israẹli yóò di iná,
    Ẹni Mímọ́ rẹ̀ yóò jẹ́ ọ̀wọ́-iná,
ní ọjọ́ kan ṣoṣo yóò jó yóò sì run
    àti ẹ̀gún àti ẹ̀wọ̀n.
18 Gbogbo ẹwà igbó o rẹ̀, àti àwọn pápá ọlọ́ràá
    gbogbo rẹ̀ ni yóò run pátápátá,
gẹ́gẹ́ bí ẹni tí ó ṣàìsàn ti í ṣòfò dànù.
19 Àwọn igi tí yóò kù nínú igbó o rẹ̀
    yóò kéré níye,
    tí ọ̀dọ́mọdé yóò fi le kọ̀ wọ́n sílẹ̀.

Àwọn ìyókù Israẹli

20 Ní ọjọ́ náà, àwọn tí ó ṣẹ́kù ní Israẹli,
    Àwọn tí ó yè ní ilé e Jakọbu,
kò ní gbẹ́kẹ̀lé ẹni náà
    tí ó lù wọ́n bolẹ̀,
ṣùgbọ́n ní òtítọ́ yóò gbẹ́kẹ̀lé Olúwa
    Ẹni Mímọ́ Israẹli.
21 Àwọn ìyókù yóò padà, àwọn ìyókù ti Jakọbu
    yóò padà sí ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Alágbára.
22 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ènìyàn rẹ, ìwọ Israẹli
    dàbí yanrìn ní Òkun,
ẹni díẹ̀ ni yóò padà.
    A ti pàṣẹ ìparun
    àkúnwọ́sílẹ̀ àti òdodo.
23 Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni yóò mú un ṣẹ,
    ìparun tí a ti pàṣẹ rẹ̀ lórí
    gbogbo ilẹ̀ náà.

24 Nítorí náà, báyìí ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí,

    “Ẹ̀yin ènìyàn mi tí ó ń gbé Sioni,
Ẹ má ṣe bẹ̀rù àwọn Asiria,
    tí ó ń fi ọ̀pá lù yín,
tí wọ́n sì ń gbé ọ̀gọ tì yín bí
    Ejibiti ti ṣe.
25 Láìpẹ́, ìbínú mi sí i yín yóò wá sí òpin
    n ó sì dojú ìrunú mi kọ wọ́n,
    fún ìparun wọn.”

26 Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò nà wọ́n ní ẹgba.
    Gẹ́gẹ́ bí ó ṣe lu Midiani
ní òkè Orebu,
    yóò sì gbé ọ̀pá rẹ̀ lé orí omi
    gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe ní Ejibiti.
27 Ní ọjọ́ náà, a ó gbé ẹrù wọn kúrò ní èjìká a yín,
    àti àjàgà a wọn kúrò ní ọrùn un yín
a ó fọ́ àjàgà náà,
    nítorí pé ẹ̀yin ó ti sanra.

28 Wọ́n wọ Aiati,
    Wọ́n gba Migroni kọjá
    Wọ́n kó nǹkan pamọ́ sí Mikmasi.
29 Wọ́n ti rékọjá ọ̀nà, wọ́n wí pé,
    “Àwa ó tẹ̀dó sí Geba lóru yìí.”
Rama mì tìtì
    Gibeah ti Saulu sálọ.
30 Gbé ohùn rẹ sókè, ìwọ ọmọbìnrin Galimu!
    Dẹ etí sílẹ̀, ìwọ Laiṣa!
    Ìwọ òtòṣì Anatoti!
31 Madmena ti fẹsẹ̀ fẹ́ ẹ
    Àwọn ènìyàn Gebimu ti fi ara pamọ́.
32 Ní ọjọ́ yìí, wọn yóò dúró ní Nobu
    wọn yóò kan sáárá,
ní òkè ọmọbìnrin Sioni
    ní òkè Jerusalẹmu.

33 Wò ó, Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun,
    yóò kán ẹ̀ka náà sọnù pẹ̀lú agbára.
Àwọn igi ọlọ́lá ni a ó gé lulẹ̀
    àwọn tí ó ga gogoro ni a ó rẹ̀ sílẹ̀.
34 Òun yóò gé igbó dídí pẹ̀lú àáké,
    Lebanoni yóò ṣubú níwájú Alágbára náà.

10 Woe(A) to those who make unjust laws,
    to those who issue oppressive decrees,(B)
to deprive(C) the poor of their rights
    and withhold justice from the oppressed of my people,(D)
making widows their prey
    and robbing the fatherless.(E)
What will you do on the day of reckoning,(F)
    when disaster(G) comes from afar?
To whom will you run for help?(H)
    Where will you leave your riches?
Nothing will remain but to cringe among the captives(I)
    or fall among the slain.(J)

Yet for all this, his anger is not turned away,(K)
    his hand is still upraised.

God’s Judgment on Assyria

“Woe(L) to the Assyrian,(M) the rod(N) of my anger,
    in whose hand is the club(O) of my wrath!(P)
I send him against a godless(Q) nation,
    I dispatch(R) him against a people who anger me,(S)
to seize loot and snatch plunder,(T)
    and to trample(U) them down like mud in the streets.
But this is not what he intends,(V)
    this is not what he has in mind;
his purpose is to destroy,
    to put an end to many nations.
‘Are not my commanders(W) all kings?’ he says.
    ‘Has not Kalno(X) fared like Carchemish?(Y)
Is not Hamath(Z) like Arpad,(AA)
    and Samaria(AB) like Damascus?(AC)
10 As my hand seized the kingdoms of the idols,(AD)
    kingdoms whose images excelled those of Jerusalem and Samaria—
11 shall I not deal with Jerusalem and her images
    as I dealt with Samaria and her idols?(AE)’”

12 When the Lord has finished all his work(AF) against Mount Zion(AG) and Jerusalem, he will say, “I will punish the king of Assyria(AH) for the willful pride(AI) of his heart and the haughty look(AJ) in his eyes. 13 For he says:

“‘By the strength of my hand(AK) I have done this,(AL)
    and by my wisdom, because I have understanding.
I removed the boundaries of nations,
    I plundered their treasures;(AM)
    like a mighty one I subdued[a] their kings.(AN)
14 As one reaches into a nest,(AO)
    so my hand reached for the wealth(AP) of the nations;
as people gather abandoned eggs,
    so I gathered all the countries;(AQ)
not one flapped a wing,
    or opened its mouth to chirp.(AR)’”

15 Does the ax raise itself above the person who swings it,
    or the saw boast against the one who uses it?(AS)
As if a rod were to wield the person who lifts it up,
    or a club(AT) brandish the one who is not wood!
16 Therefore, the Lord, the Lord Almighty,
    will send a wasting disease(AU) upon his sturdy warriors;(AV)
under his pomp(AW) a fire(AX) will be kindled
    like a blazing flame.
17 The Light of Israel will become a fire,(AY)
    their Holy One(AZ) a flame;
in a single day it will burn and consume
    his thorns(BA) and his briers.(BB)
18 The splendor of his forests(BC) and fertile fields
    it will completely destroy,(BD)
    as when a sick person wastes away.
19 And the remaining trees of his forests(BE) will be so few(BF)
    that a child could write them down.

The Remnant of Israel

20 In that day(BG) the remnant of Israel,
    the survivors(BH) of Jacob,
will no longer rely(BI) on him
    who struck them down(BJ)
but will truly rely(BK) on the Lord,
    the Holy One of Israel.(BL)
21 A remnant(BM) will return,[b](BN) a remnant of Jacob
    will return to the Mighty God.(BO)
22 Though your people be like the sand(BP) by the sea, Israel,
    only a remnant will return.(BQ)
Destruction has been decreed,(BR)
    overwhelming and righteous.
23 The Lord, the Lord Almighty, will carry out
    the destruction decreed(BS) upon the whole land.(BT)

24 Therefore this is what the Lord, the Lord Almighty, says:

“My people who live in Zion,(BU)
    do not be afraid(BV) of the Assyrians,
who beat(BW) you with a rod(BX)
    and lift up a club against you, as Egypt did.
25 Very soon(BY) my anger against you will end
    and my wrath(BZ) will be directed to their destruction.(CA)

26 The Lord Almighty will lash(CB) them with a whip,
    as when he struck down Midian(CC) at the rock of Oreb;
and he will raise his staff(CD) over the waters,(CE)
    as he did in Egypt.
27 In that day(CF) their burden(CG) will be lifted from your shoulders,
    their yoke(CH) from your neck;(CI)
the yoke(CJ) will be broken
    because you have grown so fat.[c]

28 They enter Aiath;
    they pass through Migron;(CK)
    they store supplies(CL) at Mikmash.(CM)
29 They go over the pass, and say,
    “We will camp overnight at Geba.(CN)
Ramah(CO) trembles;
    Gibeah(CP) of Saul flees.(CQ)
30 Cry out, Daughter Gallim!(CR)
    Listen, Laishah!
    Poor Anathoth!(CS)
31 Madmenah is in flight;
    the people of Gebim take cover.
32 This day they will halt at Nob;(CT)
    they will shake their fist(CU)
at the mount of Daughter Zion,(CV)
    at the hill of Jerusalem.

33 See, the Lord, the Lord Almighty,
    will lop off(CW) the boughs with great power.
The lofty trees will be felled,(CX)
    the tall(CY) ones will be brought low.(CZ)
34 He will cut down(DA) the forest thickets with an ax;
    Lebanon(DB) will fall before the Mighty One.(DC)

Footnotes

  1. Isaiah 10:13 Or treasures; / I subdued the mighty,
  2. Isaiah 10:21 Hebrew shear-jashub (see 7:3 and note); also in verse 22
  3. Isaiah 10:27 Hebrew; Septuagint broken / from your shoulders