Add parallel Print Page Options

12 (A)Nítorí náà èmi yóò fún un ní ìpín pẹ̀lú àwọn ẹni ńlá
    òun yóò sì pín ìkógun pẹ̀lú àwọn alágbára,
nítorí pé òun jọ̀wọ́ ẹ̀mí rẹ̀ fún ikú,
    tí a sì kà á mọ́ àwọn alárékọjá.
Nítorí ó ru ẹ̀ṣẹ̀ ọ̀pọ̀lọpọ̀,
    ó sì ṣe ìlàjà fún àwọn alárékọjá.

Read full chapter

12 Therefore I will give him a portion among the great,[a](A)
    and he will divide the spoils(B) with the strong,[b]
because he poured out his life unto death,(C)
    and was numbered with the transgressors.(D)
For he bore(E) the sin of many,(F)
    and made intercession(G) for the transgressors.

Read full chapter

Footnotes

  1. Isaiah 53:12 Or many
  2. Isaiah 53:12 Or numerous