Font Size
Johanu 1:4
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Johanu 1:4
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
4 (A)Nínú rẹ̀ ni ìyè wà, ìyè yìí náà sì ni ìmọ́lẹ̀ aráyé,
Read full chapter
Johanu 8:12
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Johanu 8:12
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Ẹ̀rí Jesu dájú
12 (A)Jesu sì tún sọ fún wọn pé, “Èmi ni ìmọ́lẹ̀ ayé, ẹni tí ó bá tọ̀ mí lẹ́yìn kì yóò rìn nínú òkùnkùn, ṣùgbọ́n yóò ní ìmọ́lẹ̀ ìyè.”
Read full chapter
Johanu 12:46
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Johanu 12:46
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
46 (A)Èmi ni ìmọ́lẹ̀ tí ó wá sí ayé, kí ẹnikẹ́ni tí ó bá gbà mí gbọ́ má ṣe wà nínú òkùnkùn.
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.