Add parallel Print Page Options

44 (A)Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín, ẹ ya ara yín sọ́tọ̀ kí ẹ sì jẹ́ mímọ́ torí pé mo jẹ́ mímọ́. Ẹ má ṣe sọ ara yín di àìmọ́ nípasẹ̀ ohunkóhun tí ń rìn káàkiri lórí ilẹ̀.

Read full chapter

45 Èmi ni Olúwa tí ó mú yín jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá láti jẹ́ Ọlọ́run yín torí náà, ẹ jẹ́ mímọ́ torí pé mímọ́ ni èmi.

Read full chapter

45 I am the Lord, who brought you up out of Egypt(A) to be your God;(B) therefore be holy, because I am holy.(C)

Read full chapter

(A)“ ‘Torí náà ẹ ya ara yín sí mímọ́ kí ẹ sì jẹ́ mímọ́, torí pé, èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.

Read full chapter

“‘Consecrate yourselves(A) and be holy,(B) because I am the Lord your God.(C)

Read full chapter

26 (A)Ẹ gbọdọ̀ jẹ́ mímọ́ fún mi torí pé èmi Olúwa fẹ́ mímọ́. Mó sì ti yà yín kúrò nínú àwọn orílẹ̀-èdè yòókù kí ẹ le jẹ́ tèmi.

Read full chapter

26 You are to be holy to me(A) because I, the Lord, am holy,(B) and I have set you apart from the nations(C) to be my own.

Read full chapter

16 (A)Nítorí a ti kọ ọ pé, “Ẹ jẹ́ mímọ́: nítorí tí Èmi jẹ mímọ́!”

Read full chapter

16 for it is written: “Be holy, because I am holy.”[a](A)

Read full chapter

Footnotes

  1. 1 Peter 1:16 Lev. 11:44,45; 19:2