Lefitiku 18:5
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
5 (A) Ẹ̀yin ó sì máa pa ìlànà mi mọ́ àti òfin mi; Ẹni tí ó ba ṣe, yóò yè nípa wọn: Èmi ni Olúwa.
Read full chapter
Leviticus 18:5
New International Version
Nehemiah 9:29
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
29 “Ìwọ kìlọ̀ fún wọn láti padà sínú òfin rẹ, ṣùgbọ́n wọ́n hu ìwà ìgbéraga, wọ́n sì ṣe àìgbọ́ràn si àṣẹ rẹ. Wọ́n ṣẹ̀ sí ìlànà rẹ, nípa èyí tí ènìyàn yóò yè tí wọ́n bá pa wọ́n mọ́. Nínú agídí ọkàn wọ́n kọ ẹ̀yìn sí ọ, wọ́n jẹ́ olórí kunkun wọn kò sì fẹ́ gbọ́.
Read full chapter
Nehemiah 9:29
New International Version
29 “You warned(A) them in order to turn them back to your law, but they became arrogant(B) and disobeyed your commands. They sinned against your ordinances, of which you said, ‘The person who obeys them will live by them.’(C) Stubbornly they turned their backs(D) on you, became stiff-necked(E) and refused to listen.(F)
Esekiẹli 20:11
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
11 Mo sì fún wọn ni òfin mi, mo sì fi àwọn òfin mi hàn wọ́n; nítorí pé ẹni tó bá ṣe wọ́n yóò yè nípa wọn.
Read full chapter
Ezekiel 20:11
New International Version
11 I gave them my decrees and made known to them my laws, by which the person who obeys them will live.(A)
Esekiẹli 20:13
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
13 “ ‘Síbẹ̀; ilé Israẹli ṣọ̀tẹ̀ sí mí nínú aginjù. Wọn kò tẹ̀lé àṣẹ mi, wọn sì kọ àwọn òfin mi sílẹ̀ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹni tó bá pa á mọ́ yóò yè nínú rẹ̀. Wọn sì sọ ọjọ́ ìsinmi mi di aláìmọ́ lọ́pọ̀lọpọ̀. Nítorí náà, mo sọ pé èmi yóò tú ìbínú gbígbóná mi sórí wọn, èmi yóò sì pa wọ́n run nínú aginjù.
Read full chapter
Ezekiel 20:13
New International Version
13 “‘Yet the people of Israel rebelled(A) against me in the wilderness. They did not follow my decrees but rejected my laws(B)—by which the person who obeys them will live—and they utterly desecrated my Sabbaths.(C) So I said I would pour out my wrath(D) on them and destroy(E) them in the wilderness.(F)
Esekiẹli 20:21
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
21 “ ‘Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ náà ṣọ̀tẹ̀ sí mi. Wọn kò tẹ̀lé àṣẹ mi, wọn kò sì pa òfin mi mọ́ bí o tilẹ̀ jẹ́ pé ẹni tó bá tẹ̀lé àwọn òfin yìí, yóò yè nínú rẹ̀, wọ́n sì tún sọ ọjọ́ ìsinmi mi di aláìmọ́. Nítorí náà, mo sọ pé èmi yóò tú ìbínú mi lórí wọn, Èmi yóò sì mú kí ìbínú gbígbóná mi wá sórí wọn ni aginjù.
Read full chapter
Ezekiel 20:21
New International Version
21 “‘But the children rebelled against me: They did not follow my decrees, they were not careful to keep my laws,(A) of which I said, “The person who obeys them will live by them,” and they desecrated my Sabbaths. So I said I would pour out my wrath on them and spend my anger(B) against them in the wilderness.(C)
Romu 7:10
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
10 (A)Mo ṣàkíyèsí pé òfin tí ó yẹ kí ó mú ìyè wá ni ó padà mú ikú wá.
Read full chapter
Romans 7:10
New International Version
10 I found that the very commandment that was intended to bring life(A) actually brought death.
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.
Holy Bible, New International Version®, NIV® Copyright ©1973, 1978, 1984, 2011 by Biblica, Inc.® Used by permission. All rights reserved worldwide.
NIV Reverse Interlinear Bible: English to Hebrew and English to Greek. Copyright © 2019 by Zondervan.