Font Size
Luku 13:20-21
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Luku 13:20-21
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
20 (A)Ó sì tún wí pé, “Kín ni èmi ìbá fi ìjọba Ọlọ́run wé? 21 Ó dàbí ìwúkàrà, tí obìnrin kan mú, tí ó fi sínú òṣùwọ̀n ìyẹ̀fun mẹ́ta, títí gbogbo rẹ̀ ó fi di wíwú.”
Read full chapter
Galatia 5:9
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Galatia 5:9
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
9 (A)Ìwúkàrà díẹ̀ ní í mú gbogbo ìyẹ̀fun wú.
Read full chapter
Gẹnẹsisi 18:6
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Gẹnẹsisi 18:6
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
6 Abrahamu sì yára tọ Sara aya rẹ̀ lọ nínú àgọ́, ó wí pé, “Tètè mú òṣùwọ̀n ìyẹ̀fun dáradára mẹ́ta kí o sì pò ó pọ̀, kí o sì ṣe oúnjẹ.”
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.