Font Size
Luku 21:18
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Luku 21:18
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
18 (A)Ṣùgbọ́n irun orí yín kan kì yóò ṣègbé.
Read full chapter
Ìṣe àwọn Aposteli 27:34
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Ìṣe àwọn Aposteli 27:34
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
34 Nítorí náà mo bẹ̀ yín, kí ẹ jẹun díẹ̀, nítorí èyí ni fún ìgbàlà yín: nítorí irun kan kí yóò gé kúrò lórí ẹnìkan nínú yín.”
Read full chapter
Matiu 12:12
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Matiu 12:12
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
12 Ǹjẹ́ mélòó mélòó ní ènìyàn ní iye lórí ju àgùntàn kan lọ! Nítorí náà ó yẹ láti ṣe rere ní ọjọ́ ìsinmi.”
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.