Add parallel Print Page Options

22 (A)Ó sì wí pé, “Ọmọ ènìyàn yóò jìyà ohun púpọ̀, a ó sì kọ̀ ọ́ láti ọ̀dọ̀ àwọn alàgbà, olórí àlùfáà àti láti ọ̀dọ̀ àwọn akọ̀wé, a ó sì pa á, ní ọjọ́ kẹta a ó sì jí i dìde.”

Read full chapter

22 And he said, “The Son of Man(A) must suffer many things(B) and be rejected by the elders, the chief priests and the teachers of the law,(C) and he must be killed(D) and on the third day(E) be raised to life.”(F)

Read full chapter