Font Size
Marku 13:30
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Marku 13:30
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
30 (A)Lóòótọ́ ni mo wí fún un yín, ìran yìí kì yóò rékọjá títí a ó fi mú gbogbo nǹkan wọ̀nyí ṣẹ
Read full chapter
Matiu 10:23
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Matiu 10:23
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
23 Nígbà tí wọn bá ṣe inúnibíni sì i yín ní ìlú kan, ẹ sálọ sì ìlú kejì. Lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ẹ̀yin kò tì í le la gbogbo ìlú Israẹli já tán kí Ọmọ Ènìyàn tó dé.
Read full chapter
Luku 22:18
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
Luku 22:18
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn
18 (A)Nítorí mo wí fún yín, Èmi kì yóò mu nínú èso àjàrà mọ́, títí ìjọba Ọlọ́run yóò fi dé.”
Read full chapter
Bíbélì Mímọ́ Yorùbá Òde Òn (BYO)
Copyright: Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní Ẹ̀tọ́ àdàkọ © 2009, 2017 by Biblica, Inc. A lò ó nípa ìgbàyọ̀ǹda láti ọwọ́ Bíbílíkà Inc. Ààbò lórí ẹ̀tọ́ àdàkọ yìí múlẹ̀ jákèjádò àgbáyé. Yoruba Contemporary Bible Copyright © 2009, 2017 by Biblica, Inc.® Used by permission of Biblica, Inc.® All rights reserved worldwide.