Add parallel Print Page Options

Ìsinmi fún aláàárẹ̀

25 (A)(B) Nígbà náà ni Jesu wí pé, “Mo yìn ọ Baba, Olúwa ọ̀run àti ayé, nítorí ìwọ ti fi òtítọ́ yìí pamọ́ fún àwọn tó jẹ́ ọlọ́gbọ́n àti amòye, Ìwọ sì ti fi wọ́n hàn fún àwọn ọmọ wẹ́wẹ́.

Read full chapter

The Father Revealed in the Son(A)

25 At that time Jesus said, “I praise you, Father,(B) Lord of heaven and earth, because you have hidden these things from the wise and learned, and revealed them to little children.(C)

Read full chapter

11 Ó sì da wọn lóhùn pé, “Ẹ̀yin ni a ti fi fún láti mọ ohun ìjìnlẹ̀ ìjọba ọ̀run, ṣùgbọ́n kì í ṣe fún wọn.

Read full chapter

11 He replied, “Because the knowledge of the secrets of the kingdom of heaven(A) has been given to you,(B) but not to them.

Read full chapter

17 (A)Jesu sì wí fún un pé, “Alábùkún fún ni ìwọ Simoni ọmọ Jona, nítorí ẹran-ara àti ẹ̀jẹ̀ kọ́ ló fi èyí hàn bí kò ṣe Baba mi tí ó ń bẹ ní ọ̀run.

Read full chapter

17 Jesus replied, “Blessed are you, Simon son of Jonah, for this was not revealed to you by flesh and blood,(A) but by my Father in heaven.(B)

Read full chapter

bí ó ti ṣe pé nípa ìfihàn ni ó ti fi ohun ìjìnlẹ̀ hàn fún mi gẹ́gẹ́ bí mo ti kọ ṣáájú ni ṣókí,

Read full chapter

that is, the mystery(A) made known to me by revelation,(B) as I have already written briefly.

Read full chapter

Èyí tí a kò í tí ì fihàn àwọn ọmọ ènìyàn rí nínú ìran mìíràn gbogbo, bí a ti fi wọ́n hàn nísinsin yìí fún àwọn aposteli rẹ̀ mímọ́ àti àwọn wòlíì nípa Ẹ̀mí;

Read full chapter

which was not made known to people in other generations as it has now been revealed by the Spirit to God’s holy apostles and prophets.(A)

Read full chapter