Add parallel Print Page Options

Ìsinmi fún aláàárẹ̀

25 (A)(B) Nígbà náà ni Jesu wí pé, “Mo yìn ọ Baba, Olúwa ọ̀run àti ayé, nítorí ìwọ ti fi òtítọ́ yìí pamọ́ fún àwọn tó jẹ́ ọlọ́gbọ́n àti amòye, Ìwọ sì ti fi wọ́n hàn fún àwọn ọmọ wẹ́wẹ́. 26 Bẹ́ẹ̀ ni, Baba, nítorí ó wù ọ́ láti ṣe bẹ́ẹ̀.

27 (C)“Ohun gbogbo ni Baba mi ti fi sí ìkáwọ́ mi. Kò sí ẹni tí ó mọ ọmọ bí kò ṣe Baba, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ẹnikẹ́ni tí ó mọ Baba, bí kò ṣe ọmọ, àti àwọn tí ọmọ yan láti fi ara hàn fún.

Read full chapter

The Father Revealed in the Son(A)

25 At that time Jesus said, “I praise you, Father,(B) Lord of heaven and earth, because you have hidden these things from the wise and learned, and revealed them to little children.(C) 26 Yes, Father, for this is what you were pleased to do.

27 “All things have been committed to me(D) by my Father.(E) No one knows the Son except the Father, and no one knows the Father except the Son and those to whom the Son chooses to reveal him.(F)

Read full chapter