Add parallel Print Page Options

16 (A)Ṣùgbọ́n ìbùkún ni fún ojú yín, nítorí wọ́n ríran, àti fún etí yín, nítorí ti wọ́n gbọ́. 17 Lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ọ̀pọ̀ àwọn wòlíì àti ènìyàn Ọlọ́run ti fẹ́ rí ohun tí ẹ̀yin ti rí, ki wọ́n sì gbọ́ ohun tí ẹ ti gbọ́, ṣùgbọ́n kò ṣe é ṣe fún wọn.

Read full chapter

16 But blessed are your eyes because they see, and your ears because they hear.(A) 17 For truly I tell you, many prophets and righteous people longed to see what you see(B) but did not see it, and to hear what you hear but did not hear it.

Read full chapter

16 But blessed are your eyes, for they see: and your ears, for they hear.

17 For verily I say unto you, That many prophets and righteous men have desired to see those things which ye see, and have not seen them; and to hear those things which ye hear, and have not heard them.

Read full chapter

56 (A)Abrahamu baba yín yọ̀ láti rí ọjọ́ mi: ó sì rí i, ó sì yọ̀.”

Read full chapter

56 Your father Abraham(A) rejoiced at the thought of seeing my day; he saw it(B) and was glad.”

Read full chapter

56 Your father Abraham rejoiced to see my day: and he saw it, and was glad.

Read full chapter

13 (A)Gbogbo àwọn wọ̀nyí ni ó kú nínú ìgbàgbọ́, láìrí àwọn ìlérí náà gbà, ṣùgbọ́n tí wọn rí wọn ni òkèrè réré, tí wọ́n sì gbá wọn mú, tí wọ́n sì jẹ́wọ́ pé àlejò àti àjèjì ni àwọn lórí ilẹ̀ ayé.

Read full chapter

13 All these people were still living by faith when they died. They did not receive the things promised;(A) they only saw them and welcomed them from a distance,(B) admitting that they were foreigners and strangers on earth.(C)

Read full chapter

13 These all died in faith, not having received the promises, but having seen them afar off, and were persuaded of them, and embraced them, and confessed that they were strangers and pilgrims on the earth.

Read full chapter

10 Ní ti ìgbàlà yìí, àwọn wòlíì tí wọ́n sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa oore-ọ̀fẹ́ tí ó mú tọ̀ yín wá, wọ́n wádìí jinlẹ̀ lẹ́sọ̀ lẹ́sọ̀. 11 Wọ́n ń wádìí ìgbà wo tàbí irú sá à wo ni Ẹ̀mí Kristi tí ó wà nínú wọ́n ń tọ́ka sí, nígbà tí ó jẹ́rìí ìyà Kristi àti ògo tí yóò tẹ̀lé e. 12 Àwọn ẹni tí a fihàn fún, pé kì í ṣe fún àwọn tìkára wọn, bí kò ṣe fún àwa ni wọ́n ṣe ìránṣẹ́ ohun wọ̀n-ọn-nì, tí a ti ròyìn fún yin nísinsin yìí, láti ọ̀dọ̀ àwọn tó ti ń wàásù ìhìnrere náà fún yín nípasẹ̀ Ẹ̀mí Mímọ́ tí a rán wá láti ọ̀run; ohun tí àwọn angẹli ń fẹ́ láti wò.

Read full chapter

10 Concerning this salvation, the prophets, who spoke(A) of the grace that was to come to you,(B) searched intently and with the greatest care,(C) 11 trying to find out the time and circumstances to which the Spirit of Christ(D) in them was pointing when he predicted(E) the sufferings of the Messiah and the glories that would follow. 12 It was revealed to them that they were not serving themselves but you,(F) when they spoke of the things that have now been told you by those who have preached the gospel to you(G) by the Holy Spirit sent from heaven.(H) Even angels long to look into these things.

Read full chapter

10 Of which salvation the prophets have enquired and searched diligently, who prophesied of the grace that should come unto you:

11 Searching what, or what manner of time the Spirit of Christ which was in them did signify, when it testified beforehand the sufferings of Christ, and the glory that should follow.

12 Unto whom it was revealed, that not unto themselves, but unto us they did minister the things, which are now reported unto you by them that have preached the gospel unto you with the Holy Ghost sent down from heaven; which things the angels desire to look into.

Read full chapter