Add parallel Print Page Options

26 (A)Ṣùgbọ́n Jesu wò wọ́n, ó sì wí fún wọn pé, “Ènìyàn ni èyí ṣòro fún; ṣùgbọ́n fún Ọlọ́run ohun gbogbo ni ṣíṣe.”

Read full chapter

26 Jesus looked at them and said, “With man this is impossible, but with God all things are possible.”(A)

Read full chapter

27 Jesu wò wọ́n, ó sì wí fún wọn pé, “Ènìyàn ní èyí kò ṣe é ṣe fún ṣùgbọ́n kì í ṣe fún Ọlọ́run, nítorí ohun gbogbo ni ṣíṣe fún Ọlọ́run.”

Read full chapter

27 Jesus looked at them and said, “With man this is impossible, but not with God; all things are possible with God.”(A)

Read full chapter

37 (A)Nítorí kò sí ohun tí Ọlọ́run kò le ṣe.”

Read full chapter

37 For no word from God will ever fail.”(A)

Read full chapter

(A)Nítorí ọ̀rọ̀ ìlérí ni èyí: “Ní ìwòyí àmọ́dún ni èmi yóò wá, Sara yóò sì ní ọmọ ọkùnrin.”

Read full chapter

For this was how the promise was stated: “At the appointed time I will return, and Sarah will have a son.”[a](A)

Read full chapter

Footnotes

  1. Romans 9:9 Gen. 18:10,14