Add parallel Print Page Options

13 (A)Ó wí fún wọn pé, “A sá à ti kọ ọ́ pé, ‘Ilé àdúrà ni a ó máa pe ilé mi,’ ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti sọ ọ́ di ibùdó àwọn ọlọ́ṣà.”

Read full chapter

13 “It is written,” he said to them, “‘My house will be called a house of prayer,’[a](A) but you are making it ‘a den of robbers.’[b](B)

Read full chapter

Footnotes

  1. Matthew 21:13 Isaiah 56:7
  2. Matthew 21:13 Jer. 7:11

17 (A)Gẹ́gẹ́ bí ó ti kọ́ wọn, ó wí pé, “Ṣé a kò ti kọ ọ́ pé: ‘Ilé àdúrà ni a o máa pe ilé mi, ní gbogbo orílẹ̀-èdè?’ Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti sọ ọ́ di ibùgbé àwọn ọlọ́ṣà.”

Read full chapter

17 And as he taught them, he said, “Is it not written: ‘My house will be called a house of prayer for all nations’[a]?(A) But you have made it ‘a den of robbers.’[b](B)

Read full chapter

Footnotes

  1. Mark 11:17 Isaiah 56:7
  2. Mark 11:17 Jer. 7:11

46 Ó sì wí fún wọn pé, “A ti kọ̀wé rẹ̀ pé, ‘Ilé mi yóò jẹ́ ilé àdúrà?’ Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti sọ ọ́ di ihò àwọn ọlọsa.”

Read full chapter

46 “It is written,” he said to them, “‘My house will be a house of prayer’[a];(A) but you have made it ‘a den of robbers.’[b](B)

Read full chapter

Footnotes

  1. Luke 19:46 Isaiah 56:7
  2. Luke 19:46 Jer. 7:11