Add parallel Print Page Options

37 (A)“Jerusalẹmu, Jerusalẹmu, ìlú tí ó pa àwọn wòlíì, tí ó sì sọ òkúta lu àwọn tí a rán sí i. Ọ̀pọ̀ ìgbà ni èmi tí ń fẹ́ kó àwọn ọmọ rẹ jọ pọ̀ gẹ́gẹ́ bí àgbébọ̀ adìyẹ ti í dáàbò bo àwọn ọmọ rẹ̀ lábẹ́ ìyẹ́ rẹ, ṣùgbọ́n ẹ̀yin kọ̀. 38 Wò ó, a fi ilé yín sílẹ̀ fún yín ní ahoro. 39 Nítorí èmi sọ èyí fún yín, ẹ̀yin kì yóò rí mi mọ́, títí ẹ̀yin yóò fi sọ pé ‘Olùbùkún ni ẹni tó ń bọ̀ ní orúkọ Olúwa.’ ”

Read full chapter

37 “Jerusalem, Jerusalem, you who kill the prophets and stone those sent to you,(A) how often I have longed to gather your children together, as a hen gathers her chicks under her wings,(B) and you were not willing. 38 Look, your house is left to you desolate.(C) 39 For I tell you, you will not see me again until you say, ‘Blessed is he who comes in the name of the Lord.’[a](D)

Read full chapter

Footnotes

  1. Matthew 23:39 Psalm 118:26

41 (A)Nígbà tí ó sì súnmọ́ etílé, ó ṣíjú wo ìlú náà, ó sọkún sí i lórí,

Read full chapter

41 As he approached Jerusalem and saw the city, he wept over it(A)

Read full chapter