Add parallel Print Page Options

20 Dípò bẹ́ẹ̀ to ìṣúra rẹ jọ sí ọ̀run, níbi ti kòkòrò àti ìpáàrà kò ti lè bà á jẹ́, àti ní ibi tí àwọn olè kò le fọ́ wọlé láti jí í lọ.

Read full chapter

20 But store up for yourselves treasures in heaven,(A) where moths and vermin do not destroy, and where thieves do not break in and steal.(B)

Read full chapter

33 (A)Ẹ ta ohun tí ẹ̀yin ní, kí ẹ sì tọrẹ àánú kí ẹ sì pèsè àpò fún ara yín, tí kì í gbó, ìṣúra ní ọ̀run tí kì í tán, ní ibi tí olè kò lè súnmọ́, àti ibi tí kòkòrò kì í bà á jẹ́.

Read full chapter

33 Sell your possessions and give to the poor.(A) Provide purses for yourselves that will not wear out, a treasure in heaven(B) that will never fail, where no thief comes near and no moth destroys.(C)

Read full chapter

45 Wọn si ń ta ohun ìní àti ẹrù wọn, wọn sì ń pín wọn fún olúkúlùkù, gẹ́gẹ́ bí ẹnikẹ́ni tí í ṣe aláìní sí.

Read full chapter

45 They sold property and possessions to give to anyone who had need.(A)

Read full chapter

34 Nítorí kò sí ẹnìkan nínú wọn tí ó ṣe aláìní, nítorí iye àwọn tí ó ní ilẹ̀ tàbí ilé tà wọ́n, wọ́n sì mú owó ohun tí wọn tà wá. 35 Wọ́n sì fi í lélẹ̀ lẹ́sẹ̀ àwọn aposteli, wọn sì ń pín fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe aláìní sí.

Read full chapter

34 that there were no needy persons among them. For from time to time those who owned land or houses sold them,(A) brought the money from the sales 35 and put it at the apostles’ feet,(B) and it was distributed to anyone who had need.(C)

Read full chapter