Add parallel Print Page Options

15 Jesu sì dáhùn pé, “Àwọn ọmọ ilé ìyàwó ha le máa ṣọ̀fọ̀, nígbà tí ọkọ ìyàwó ń bẹ lọ́dọ̀ wọn? Ṣùgbọ́n ọjọ́ ń bọ̀ nígbà tí a ó gba ọkọ ìyàwó lọ́wọ́ wọn; nígbà náà ni wọn yóò gbààwẹ̀.

Read full chapter

15 Jesus answered, “How can the guests of the bridegroom mourn while he is with them?(A) The time will come when the bridegroom will be taken from them; then they will fast.(B)

Read full chapter

20 (A)Ṣùgbọ́n láìpẹ́ ọjọ́, a ó gba ọkọ ìyàwó kúrò lọ́dọ̀ wọn. Nígbà náà wọn yóò gbààwẹ̀ ni ọjọ́ wọ̀nyí.”

Read full chapter

20 But the time will come when the bridegroom will be taken from them,(A) and on that day they will fast.

Read full chapter

35 Ṣùgbọ́n àkókò ń bọ̀ nígbà tí a ó gba ọkọ ìyàwó kúrò lọ́dọ̀ wọn, ní àwọn ọjọ́ wọ̀nyí ni wọn yóò gbààwẹ̀.”

Read full chapter

35 But the time will come when the bridegroom will be taken from them;(A) in those days they will fast.”

Read full chapter