Add parallel Print Page Options

17 (A)Nítorí nínú ìhìnrere ni òdodo Ọlọ́run ti farahàn, òdodo Ọlọ́run nípa ìgbàgbọ́ láti ìbẹ̀rẹ̀ dé òpin gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ nínú ìwé Mímọ́ pé, “Olódodo yóò yè nípa ìgbàgbọ́ rẹ̀.”

Read full chapter

17 For in the gospel the righteousness of God is revealed(A)—a righteousness that is by faith(B) from first to last,[a] just as it is written: “The righteous will live by faith.”[b](C)

Read full chapter

Footnotes

  1. Romans 1:17 Or is from faith to faith
  2. Romans 1:17 Hab. 2:4