Add parallel Print Page Options

Orin fún ìgòkè. Ti Dafidi.

124 “Ìbá má ṣe pé Olúwa tí ó ti wà fún wa”
    ni kí Israẹli kí ó máa wí nísinsin yìí;
“Ìbá má ṣe pé Olúwa tó wà ní tiwa,”
    Nígbà tí àwọn ènìyàn dúró sí wa:
Nígbà náà ni wọn ò bá gbé wà mì láààyè
    nígbà tí ìbínú wọn ru sí wa
Nígbà náà ni omi
    wọ̀n-ọn-nì ìbá bò wá mọ́lẹ̀
Nígbà náà ni agbéraga
omi ìbá borí ọkàn wa.

Olùbùkún ni Olúwa, tí kò fi wá fún wọ́n
    bí ohun ọdẹ fún eyín wọn.
Ọkàn wa yọ bí ẹyẹ jáde kúrò nínú okùn apẹyẹ;
    okùn já àwa sì yọ.
Ìrànlọ́wọ́ wa ń bẹ ní orúkọ Olúwa,
    tí ó dá ọ̀run òun ayé.

Psalm 124

A song of ascents. Of David.

If the Lord had not been on our side—
    let Israel say(A)
if the Lord had not been on our side
    when people attacked us,
they would have swallowed us alive
    when their anger flared against us;
the flood(B) would have engulfed us,
    the torrent(C) would have swept over us,
the raging waters
    would have swept us away.

Praise be to the Lord,
    who has not let us be torn by their teeth.
We have escaped like a bird
    from the fowler’s snare;(D)
the snare has been broken,(E)
    and we have escaped.
Our help is in the name(F) of the Lord,
    the Maker of heaven(G) and earth.