Add parallel Print Page Options

Ohùn Olúwa n ré àwọn omi kọjá;
    Ọlọ́run ògo sán àrá,
    Olúwa san ara.

Read full chapter

The voice(A) of the Lord is over the waters;
    the God of glory(B) thunders,(C)
    the Lord thunders over the mighty waters.(D)

Read full chapter

31 Tẹra sì mú ọmọ rẹ̀ Abramu àti Lọti ọmọ Harani, ọmọ ọmọ rẹ̀, ó sì mú Sarai tí i ṣe aya ọmọ rẹ̀. Abramu pẹ̀lú gbogbo wọn sì jáde kúrò ní Uri ti Kaldea láti lọ sí ilẹ̀ Kenaani. Ṣùgbọ́n nígbà tí wọn dé Harani wọ́n tẹ̀dó síbẹ̀.

Read full chapter

31 Terah took his son Abram, his grandson Lot(A) son of Haran, and his daughter-in-law(B) Sarai, the wife of his son Abram, and together they set out from Ur of the Chaldeans(C) to go to Canaan.(D) But when they came to Harran,(E) they settled there.

Read full chapter

Ó sì tún wí fún un pé, “Èmi ni Olúwa tí ó mú ọ jáde láti Uri ti Kaldea láti fún ọ ní ilẹ̀ yìí láti jogún.”

Read full chapter

He also said to him, “I am the Lord, who brought you out(A) of Ur of the Chaldeans(B) to give you this land to take possession of it.”(C)

Read full chapter