Add parallel Print Page Options

(A)Àwọn tí ó kórìíra mi láìnídìí
    wọ́n ju irun orí mi; lọ
púpọ̀ ni àwọn ọ̀tá mi láìnídìí,
    àwọn tí ń wá láti pa mí run
A fi ipá mú mi
    láti san ohun tí èmi kò jí.

Read full chapter

Those who hate me(A) without reason(B)
    outnumber the hairs of my head;
many are my enemies without cause,(C)
    those who seek to destroy me.(D)
I am forced to restore
    what I did not steal.

Read full chapter

25 (A)Ṣùgbọ́n èyí rí bẹ́ẹ̀ kí ọ̀rọ̀ tí a kọ nínú òfin wọn kí ó lè ṣẹ pé, ‘Wọ́n kórìíra mi ní àìnídìí.’

Read full chapter

25 But this is to fulfill what is written in their Law:(A) ‘They hated me without reason.’[a](B)

Read full chapter

Footnotes

  1. John 15:25 Psalms 35:19; 69:4